O ba’le gude! Ohun mimu ti n fun’ni l’agbara POWER BLACK ENERGY DRINK wo’le...

0
Nkan mimu elerindodo ti oruko re n je POWER BLACK ENERGY DRINK ni won ti ko s'ita bi omo ojo mejo l'eko lojo Tuiside...

Kokumo: Ope o! Omo Iyabo-Oko ni Iya oun o ku mo o

0
Agba osere tiata nni, ti Eledua fun lebun ere sise pupo, iyen Sidikat Odukanwi, ti gbogbo aye mo si IyaboOko, ni omo re, Bisi...

OmiTeyinWo’gbinL’enu: Oye Olubadan le ma bo s’owo Lekan Balogun mo o. Idi re

0
Gomina ana, Oloye Rasidi Ladoja ni o se e se ko di Olubadan tuntun

E w’oju baba ti oye Olubadan yi kan bayi

0
Gege bi isedale ilu Ibadan, oye Olubadan kii se ti idile kan ni pato bi won ti ma n se ni awon ilu Yoruba...

Keere o…. Olubadan w’aja!

0
Kaabiyesi Olubadan ti ilu Ibadan, Oba Saliu Adetunji ti darapo mo awon baba nla re l’eni odun metalelaadorun (93). IROYIN YII NA LE WU O...

Lori oro Olori Ooni to ja’we fun Kaabiyesi, Elebuibon ni o di dandan ki...

0
Ogbontarigi Babalawo to gbo’fa yanranyanran, to tun je Araba ti ilu osogbo, iyen Baba Yemi Elebuibon ti se afomo oro wipe Olori-k’olori to ba...

Awon Olopa ju Osere tiata s’atimole l’Abule-Egba

0
O se e se ki owo awon olopa ti te gbajugbaja osere tita nni, Damola Olatunji leyin ti o fi esun kan awon agbofinro...

“Abẹrẹ-ajesara lásán o le ko orilẹ-èdè kankan yo nínú laasigbo Omikuronu” -Ajo WHO lo...

0
Ajo to n mojuto ètò ilera l'agbaye, ìyẹn World Health Organisation (WHO) lo ti n kọminu wípé eya korona-fairosi ti wọn n pe Omikuronu...

“On’iro aye at’orun gba-a ni Bisi Akande” –Ayo Adebanjo lo so be

0
Olori egbe Afenifere, Oloye Ayo Adebanjo ti fi enu-ate ba iwe kan ti Aare egbe APC nigba kan ri, Bisi Akande gbe jade l’ose...

Erin wo! Soun Ogbomoso w’aja

0
Kabiyesi, Soun ti ilu Ogbomoso Oba Jimoh Oyewumi (Ajagungbade 1) ti w’aja leyin odun mejidinlaadota (48) ti won ti wa lori apere. Ojo kerilelogun...

Stay connected

0FansLike
3,790FollowersFollow
0SubscribersSubscribe
- Advertisement -

Latest article

Odunlade Adekola preaches Health Insurance benefits in Ijebu-Ode Markets, Parks

0
The ace Nollywood actor, Odunlade Adekola has urged residents of Ijebu-Ode in Ogun State to embrace the health insurance scheme introduced by the Prince...

Two Nigerians in Diaspora mobilise Pelican Valley to full construction on Pelican Brief Estate,Kobape

0
Two Nigerians in Diaspora,Chief Olawale Olaleye and Mrs Najiyat have mobilized the construction team of Pelican Valley Estate, Kobape , Ogun State to commence...

Ogun House of Assembly workers begin indefinite strike

0
Workers in Ogun Assembly under the aegis of the Parliamentary Staff Association of Nigeria (PASAN) have declared indefinite strike action beginning from Thursday over...